BBC News, Yorùbá – Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó

Fayose nílò àdúrà, ẹ ṣàánú rẹ̀ – Makinde da padà lẹ́yìn tí Fayose ní ó lè jẹ́ òun ló ṣagbátẹrù ìjínigbé Ogbomoso
Ninu atẹjade kan ti kọmiṣọna fun iroyin ipinlẹ Oyo, Dotun Oyelade fi lede lorukọ gomina Seyi Makinde, o ni iyalẹnu nla ni ẹsun ti Fayose fi kan Makinde jẹ.
wákàtí 5 sẹ́yìn

Àwọn ilé ẹ̀kọ́ tilẹ̀kùn wọn pa l’Osun nítorí ìròyìn pé agbébọn wọ ìlú, Adeleke ní kò sí ohun tó jọ bẹ́ẹ̀
Adeleke ni awọn ọta ilu atawọn ọmọ ẹgbẹ alatako lo n gbe iroyin ẹlẹjẹ naa iri.
wákàtí 7 sẹ́yìn

Aráàlú fárígá, àwọn olùwọ́de já géètì sẹkitéríàtì ìjọba, ìpè fún ìtúsílẹ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l’Ogbomoso káàkiri Nàìjíríà
Awọn eeyan naa ti wọn ko ara wọn lati fi aidunnu wọn han si bawọn eeyan naa ṣe wa ni akata awọn ajinigbe lati ọjọ kẹẹdogun oṣu Karun un ti kọja, bẹnu ẹtẹ lu bi ijọba ko ṣe tii ri wọn doola.
wákàtí 9 sẹ́yìn

Ìjàmbá ọkọ̀ ló fa ikú òṣèré tíátà, ‘Janmole’ – Mr Latin
Aarẹ ẹgbẹ awọn oṣere TAMPAN, Ọgbẹni Bolaji Amusan, tawọn eeyan mọ si Mr Latin lo fi iroyin iku naa lede loju opo Instagram rẹ.
wákàtí 8 sẹ́yìn
0:56
Orin, Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́, Duration 0,56
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́
wákàtí 8 sẹ́yìn

Èyí làwọn olóṣèlú tó fẹ́ dupò ààrẹ ní 2027 tórúkọ wọn gbilẹ̀ jù
Awọn ẹgbẹ alatako torukọ wọn gbilẹ ju ni ADC, NDC ati PDP
2 Òkùdu 2026

Fídíò, Aṣọ kan ló kù lọ́rùn àwọn òbí mi nítorí ẹ̀kọ́ mi, ètò ẹ̀yáwókàwé NELFUND ló kó mi yọ láti kẹ́kọ̀ọ́ jáde – Oladepo Gbenga akẹ́kọ̀ọ́ tó mókè jùlọ ní fásitì LAUTECH
Arakunrin naa ni àwọn obi oun talaka ju ekute ṣọọṣi lọ nitori ati kẹkọọ oun atawọn ẹgbọn ati abura.
2 Òkùdu 2026

Àwọn wo ló fẹ́ wú ère ẹlẹ́sẹ̀ ayò, Lionel Messi, àti pé kí ló fàá?
Ere giga naa to wa ni Kolkata, ni West Bengal ni wọn gbe kalẹ ninu oṣu Kẹwaa ti Messi rinrinajo ‘GOAT’ lọ sorilẹede ọhun.
2 Òkùdu 2026

Àwọn orílẹ̀èdè Áfríkà wo ló jẹ àjọ IMF lówó jùlọ ?
Bi o tilẹ jẹ pe awọn orilẹede maa n lo owooya lati ajọ IMF lati fi ṣe eto ọrọ aje wọn, ẹru wiwo gbese ọlọjọ gbọọrọ lee bẹgidina idagbasoke.
1 Òkùdu 2026

Kókó ohun tó jẹyọ lásìkò àbẹ̀wò ìgbìmọ ìjọba àpapọ̀ sí Ogbomoso lórí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àtàwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé
Igbimọ naa kọminu lori iṣẹlẹ ọhun, wọn si ṣeleri pe Aarẹ Bola Tinubu yoo sa gbogbo agbara rẹ lati doola gbogbo awọn ti wọn ji gbe.
1 Òkùdu 2026

Ẹgbẹ́ olùkọ́ bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì l’Oyo lórí àwọn tí wọ́n jí gbé l’Ogbomoso, Tinubu kéde ìgbésẹ láti gba aṣógbó 1,000 síṣẹ́
Ṣaaju ni ẹgbẹ NUT ti sọ fawọn ọmọ ẹgbẹ naa nipinlẹ Oyo wi pe ki wọn ṣe ifẹhonuhan lati beere fun itusilẹ awọn tawọn janduku agbebọn ji gbe.
1 Òkùdu 2026

Ìfẹ̀hónúhàn bẹ́ sílẹ̀ ní France lẹ́yìn tí PSG gba ife ẹ̀yẹ Champions League, èèyàn 219 farapa
A gbọ pe eeyan mẹjọ lo wa ni ẹsẹ kan aye ẹsẹ kan ọrun gẹgẹ bii ọrọ minisita fun ọrọ abẹle, Laurent Nuñez.
31 Èbibi 2026
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
00:37 Fídíò, Aráàlú fárígá, ṣèwọ́de ní Ibadan tako ìjọba lórí bí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ tí wọ́n jí gbé ṣì ṣe wà ní àhámọ́ , Duration 0,37
02:45 Fídíò, Ìfúpá àwọn èèyàn Ayetoro l‘Ondo ń ga sí, torí bí òkun ṣe ń ya wọ ìlú, gbé iléẹ̀kọ́, ilégbèé, iléeṣẹ́, ilẹ̀ àti ibojì òkù lọ, Duration 2,45
01:26 Fídíò, Wo àkóbá mọ́kànlá tí ohun mímu ‘Energy Drinks’ le ṣe fún àgọ́ ara rẹ, Duration 1,26
04:32 Fídíò, Ìjì òjò líle sí òrúlé, da ògiri wó nílé ẹ̀kọ́ girama ọgbọ̀n l‘Ogbomoso, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ n kẹ́kọ̀ọ́ lábẹ́ ilé àlàpa, Duration 4,32
02:16 Fídíò, “Ìjọba rí epo rọ̀bì ní ìlú wa àmọ́ a kò jàǹfààní kankan, kò sí omi, iná, ojú ọ̀nà, ààbò, iléẹ̀kọ́ àti ilé ìwòsàn”, Duration 2,16
03:22 Fídíò, Àwọn ajínigbé tó kó àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yìnbọn sí wa nígbà tí a ń lé wọn wọgbó ìbọn wà kò ràn wọ́n ni – Àwọn ọlọ́dẹ ìlú Esinele, Duration 3,22
02:31 Fídíò, Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àrùn Ebola tuntun, Duration 2,31
02:34 Fídíò, Oronna, jagunjagun tó gbéra láti Oyo lọ tẹ ìlú Ilaro dó, Duration 2,34
02:21 Fídíò, Olaniyan ‘Idamu Industry’ Oluwatosin jẹ́wọ́ pé ẹnu nìkan kọ́ lòun ní lórí ètò ‘Ṣé o láyà?’, Duration 2,21
05:24 Fídíò, Agbolé Akọni: Mọ̀ nípa Ogboriefon, akọni tí wọ́n rí he lórí àkìtàn tó di jagunjagun ńlá, Duration 5,24
01:40 Fídíò, Wo bí hòmóònù ṣe ń mú àyípadà bá ìhùwàsí àwọn obìnrin ní ọ̀sọ̀ọ̀sẹ̀, Duration 1,40
04:05 Fídíò, Mo ti fẹ́ obìnrin rí lágbo tíátà àmọ́ kò ní àṣeyọrí, owó, obìnrin àti agbára ló ń fa gbajúmọ̀ ọkùnrin ṣubú – Abayomi Alvin, Duration 4,05
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

‘A ò lè lọ síbi iṣẹ́ mọ́ torí àwọn olùkọ́ àtàwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l’Ogbomoso,’ àwọn olùkọ́ ṣèfẹ̀hónúhàn l’Oyo
Awọn olukọ naa bẹrẹ iwọde wọn lati agbegbe Iwo road niluu Ibadan ti wọn si gba Idi-ape, Gate titi de ọfiisi ijọba Ipinlẹ Oyo ni Agodi niluu ibadan.
30 Èbibi 2026

Báwo ni ayẹyẹ Ojude Oba 2026 ṣe rí láì sí Awujale Ijebu lórí oyè? Ohun tó ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ rèé
Ṣaaju eto ayeye ọdun ọhun to waye lọjọ Ẹti, ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu Karun-un ti a wa yii, ni oniruuru awuyewuye ti n waye lori boya eto naa ko ni waye lọdun yii.
30 Èbibi 2026

Ilé ìgbìmọ̀ àṣofin Ghana buwọ́lu òfin tó kéde ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́ta fún ìbálòpọ̀ akọsákọ àti abosábo
Ofin tuntun ọhun tun ke pe araalu lati fi to ijọba leti ti wọn ba kofiri ẹnikẹni to ba n ṣe nnkan naa ti wọn ti fofin de.
30 Èbibi 2026

Àgbà òṣèré tíátà, Feso Oyewole jáde láyé
Awọn mọlẹbi oloogbe naa lo kede iroyin iku rẹ ninu atẹjade kan lọjọ Abamẹta.
30 Èbibi 2026

Taa ni Balogun Kuku, bàbá olówó tó mú ẹ̀sìn Islam wọ ilẹ̀ Ijebu, tó tún bẹ̀rẹ̀ ọdún Ojude Ọba?
Itan igbe aye Balogun Bello Kuku, ẹni to mu Islam wọ ilẹ Ijẹbu, to si tun bẹrẹ ayẹyẹ ọdun Ojude Oba to di gbaju-gbaja ni Ijebu Ode.
28 Èbibi 2026

Kí ni pàtàkì Òkúta Dúdú táwọn olùjọsìn máa ń fọwọ́ kan tàbí fẹnu kò ní Kaaba lásìkò Hajj?
Lọdọọdun ni ọpọ eeyan maa n ti ara wọn, koda wọn maa n tẹ awọn mii mọlẹ nibẹ lati ri pe awọn lanfaani lati fọwọ kan okuta naa.
28 Èbibi 2026

Àlàyé rèé lórí bí fọ́nrán ohùn Tinubu tí wọ́n fi AI ṣe, ṣe dá wàhálà sí VDM lọ́rùn, tí wọn ṣí ló gbọdọ̀ fojú winá òfin
Bi AI ṣe wulo lati mu iṣẹ ya kankan, bẹẹ naa ni awọn to mọ lilo rẹ nidakeji tun maa n lo o lati ya fidio eeyan tabi lo ohùn ẹnu ẹni ti wọn ba fẹ fi ṣe jamba fun.
28 Èbibi 2026

Ìtàn mánigbàgbé: Bí ilà kíkọ ṣe bẹ̀rẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá àti bí wọn ṣe fi ilà kíkọ kó ìlú kan lógun
BBC News Yorùbá ṣe wọ inú ìtàn lọ, láti ṣe ilanilọyẹ lórí ohun tó fà á, tí ìran Yoruba ṣe ń kọ ila àti bí wọn ṣe fi ilà kíkọ kó ìlú kan lógun.
29 Èbibi 2026

Aṣọ oníbúrẹ́dì 500 tí mo wọ lọ síbi àmì ẹ̀yẹ AMVCA dá egbò sí mi lẹ́yìn, mú ẹ̀yìn ro mi, ó jẹ́ kí n fara ṣèṣe – Queen Mercy
Nigba to n sọrọ, Mercy ni oun kọ loun ran aṣọ naa, bi ko ṣe gbajumọ aranṣọ Toyin Lawani to jẹ ọga ileeṣẹ Tianah Empire.
29 Èbibi 2026

Iran ṣàlàyé ìdí abájọ tó fi ṣèkọlù sí ibùdó ológun Amẹrika
Ajọ IRGC ni oun ṣekọlu si ibudo naa lẹyin ti Amẹrika yin ado oloro si ẹkun guusu Iran.
29 Èbibi 2026

Àlàyé rèé nípa fọ́tò tó ṣàfihàn Ààrẹ Tinubu tó kúnlẹ̀ níta gbangba, tí pásítọ̀ gbọ́wọ́ lé e lórí
Ninu ọsẹ yii naa ni ọrọ fọnran ohun ti wọn fi AI gbe jade bọ sori ayelujara, nibi ti wọn ti fi ohùn ẹnu Tinubu sọ awọn ọrọ to n tako araalu, to si le da rugudu silẹ.
29 Èbibi 2026

Wo kókó ohun mọ́kànlá tí Tinubu fi ránṣẹ́ sọ́mọ Náíjíríà lórí ààbò àti ọrọ̀ ajé láti sàmì ọdún kẹta rẹ̀ nípò ààrẹ
Aarẹ Bola Tinubu ni yiyọ owo iranwọ ori epo, riro owo naira lagbara lọja agbaye ati gbigbe ogun ti aabo to mẹhẹ ti oun dawọle, ti so eso rere.
29 Èbibi 2026

Agbébọn jí ajagunfẹ̀yìntì àti ìyàwọ rẹ̀ gbé ní Katsina
31 Èbibi 2026

Makinde ṣàbẹ̀wò sẹ́bí àwọn èèyàn tí wọ́n jí gbé l’Ogbomoso, ọkọ Ọ̀gá ilé ẹ̀kọ́ tí wọ́n gbé bú sẹ́kún
31 Èbibi 2026

Ẹgbẹ́ àwọn gómìnà bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti máa san ₦100,000 gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù òṣìṣẹ́ tó kéré jùlọ
31 Èbibi 2026

“Ẹ jọ̀ọ́ ẹ má jẹ́ kí wọ́n fi ẹ̀mí wa ṣòfò,” àwọn olùkọ́ tí agbésùnmọ̀mí jígbé l’Ogbomoso rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí ìjọba
30 Èbibi 2026

”Èyi ni ipa tí Bàba-bàbá mi kó nínú ogun abẹ́lé Biafra”-Meji Alabi, gbajúmọ̀ adarí orin
1 Òkùdu 2026

Ta ló yẹ kó pa ẹran Ileya, ṣé ẹ̀ṣẹ̀ wà fún ẹni tí kò bá pa ẹran, kí ni ẹni tó bá fẹ́ pa ẹran gbọdọ̀ ṣe?
27 Èbibi 2026

Arafat Day: Wo ohun márùn-ún tí ayájọ́ òní fi lọ́lá jùlọ nínú Islam
26 Èbibi 2026

Ẹbí Alexx Ekubo sọ̀rọ̀ lórí irúfẹ́ jẹjẹrẹ kíndìnrín tó sokùnfa ikú rẹ̀
14 Èbibi 2026
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára

Ìbẹ̀rù gbalẹ̀ kan bí àrùn Ebola ṣe rán èèyàn 100 sọ́run ọ̀sánangan
25 Èbibi 2026
1:21
Fídíò, Wo atọ́kùn ètò móhùnmáwòrán tó ṣe àfihàn bí wọ́n ṣe ń yin ìbọn AK-47 lórí afẹ́fẹ́, Duration 1,21
23 Èbibi 2026

‘Rògbòdìyàn ìdìbò 1983 kó wàhálà tó pọ̀ bá ẹbí mi nítorí bàbá mi díje, ṣùgbọ́n ìfẹ́ àráàlú ló mú mifẹ́ di gómìnà Ekiti’
22 Èbibi 2026
1:48
Fídíò, ‘Fóònù àti tẹlifíṣàn àwòjù le è ṣe àkóbá fún ọpọlọ ọmọ rẹ’, Duration 1,48
21 Èbibi 2026
4:06
Fídíò, Ìdí tí Tòmátò ẹ̀sà kò ṣe dára fún ìlera yín; wo àwọn kókó márùn-ún yìí, Duration 4,06
18 Èbibi 2026
1:02
Fídíò, Sola Sobowale àti Lateef Adedimeji sọ̀rọ̀ lórí àmì ẹ̀yẹ AMVCA tí wọn gbà, Duration 1,02
13 Èbibi 2026
5:59
Fídíò, Ṣọ́ọ̀ṣì kan rèé tí wọn kií lanu sọ̀rọ̀, ọwọ́ lásán làwọn akọrin, oníwàásù àti olùjọ́sìn fi ń júwe, Duration 5,59
12 Èbibi 2026
0:52
Fídíò, Àwọn aṣọ aláràmbarà tí wọ́n lò níbi ayẹyẹ AMVCA, Duration 0,52
12 Èbibi 2026

Ìrọ́ ni pé PDP dara pọ̀ mọ́ APM l‘Oyo, ẹgbẹ́ wa tóbi ju ká dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú kankan lọ, àwa lá borí ìbò ààrẹ – Gbolarumi
BBC News Yoruba ba Amofin Azeem Gbolarumi sọrọ ni kete to wọle ibo abẹle PDP bii oludije gomina fẹgbẹ PDP nipinlẹ Oyo.
26 Èbibi 2026

Ọlọ́pàá méjì kú ní ìpínlẹ̀ Osun lẹ́yìn tí ọkọ̀ gbá wọn lójú pópó
Ọlọpaa orukọ awọn ọlọpaa meji ti ọrọ naa kan lede gẹgẹ bii Kehinde ati Tobi lai mẹnuba orukọ wọn keji.
30 Èbibi 2026

Ìjà abẹnú ADC fẹjú síi, igun kan kẹ̀yìn sí David Mark, yan Dumebi Kachikwu bíi olùdíje ààrẹ, bí igun Mark ṣe fẹ́ yan olùdíje aarẹ lónìí
Ana ode yiii ti I ṣe ọjọ Aiku, ọjọ kẹrinlelogun oṣu Karun-un ọdun 2026, ni igun tuntun yi tu igbimọ amuṣẹṣe ‘National working committee’ (NWC) ti David Mark n dari ka, ti wọn si yan Dumebi Kachikwu lẹyẹ o-sọka.
25 Èbibi 2026

“Ọ̀rọ̀ aláàgànná àti ọlọ́tí ni pé Oluwo wú òkú àwọn ọba tí wọ́n sín sí ààfin rẹ̀, ṣe ló tún ibòji wọn ṣe”
Awọn eeyan to sunmọ ọba Akanbi, ti wọn si mọ awọn ohun to ṣẹlẹ nipa awọn oju oori yii ti n ṣe alaye tiwọn.
27 Èbibi 2026

Àjọ NEMA kéde agbègbè 37 tó wà nínú ewu ẹ̀kún omi, 15 l’Eko, 19 l’Ogun, 3 ní Nassarawa
NEMA ni kawọn to ba n gbe ni bebe okun lagbegbe naa tete fi ibẹ silẹ
27 Èbibi 2026

Ta ló wọlé ìbò abẹ́nú ẹgbẹ́ òṣèlú Accord láti dupò Gómìnà l’Oyo láàrin Oriyomi àti Gudugudu? Ohun tí a mọ̀ rèé
Ṣaaju eto idibo naa ni ọkan lara awọn oludije ninu mẹta sipo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu Accord, Fatai Owoseni, juwọ silẹ pe oun ko dije mọ.
27 Èbibi 2026

Tinubu wọlé ìbò abẹ́nú APC láti díje fún ipò ààrẹ lẹ́ẹ̀kejì, iye ìbò tó rí rèé
Sẹnẹtọ Pius Anyim lo kede esi ibo naa lonii ọjọ Aiku ọjọ kẹrinlelogun oṣu Karun un yii.
24 Èbibi 2026

Afurasí tó fẹ́ kó àwọn ọmọdé lọ ṣiṣẹ́ aṣẹ́wó ní Ghana rí ẹ̀wọ̀n ọdún méjìlá he l’Ogun
Awọn ọmọde naa bi kootu ṣe darukọ wọn ni Bright Edim, ọmọ ọdun mẹẹẹdogun ati Mary Ekong toun naa jẹ ọmọ ọdun mẹẹẹdogun (15) bakan naa.
24 Èbibi 2026

AI lè gba iṣẹ́ lọ́wọ́ àwọn èèyàn tí kò bá fi kún ìmọ̀ ẹ̀rọ wọn lẹ́nu iṣẹ́ ọba-Ìjọba àpapọ̀
Bo tilẹ jẹ pe ijọba tun fi awọn oṣiṣẹ lọkan balẹ pe lilo AI ko tumọ si pe yoo rọpo awọn eeyan patapata, sibẹ, o ṣee ṣe kawọn kan padanu iṣẹ wọn.
24 Èbibi 2026

Wo bí àwọn alátìlẹyìn Arsenal ṣe ń ṣàjọyọ̀ lẹ́yìn tí wọ́n gba ife ẹ̀yẹ Premier League lẹ́yìn ọdún 22
20 Èbibi 2026
3:29
Fídíò, “Eré ìdárayá ìgbátí ni mo fi ń jẹun, wọ́n ti gbá mi léti rí tí ojú mi ya, mo sojú Nàíjíríà nínú ìdíje àgbáyé”, Duration 3,29
11 Èbibi 2026

Àlàyé lórí ọjọ́, pápá ìṣiré àti àkókò tí àṣekágbá ife ẹ̀yẹ UEFA Champions League tí Arsenal fẹ́ gbá yóò wáyé?
6 Èbibi 2026

Ẹ wo bi ìjà Portable àti Carter Efe ṣe lọ nílùú Eko
2 Èbibi 2026

Ọkọ̀ tó kó àwọn agbábọ́ọ̀lù pàdé àwọn adigunjalè lọ́nà, wọ́n yìnbọn pa agbábọ́ọ̀lù kan
14 Ìgbé 2026

Senegal yóò ṣàfihàn Ife ẹ̀yẹ AFCON 2025 lópin ọ̀sẹ̀ yìí, bó tilẹ̀ jẹ́ pé CAF ti gbé ife náà fún Morocco
27 Ẹrẹ̀nà 2026

CAF gba ife ẹ̀yẹ AFCON 2025 lọ́wọ́ Senegal, gbé e fún Morocco
17 Ẹrẹ̀nà 2026

Adegboye Onigbinde akọ́nimọ̀ọ́gbá Super Eagles tẹ́lẹ̀ jáde láyé lẹ́ni ọdún 88
10 Ẹrẹ̀nà 2026

Télọ̀ kan ju èké fídíò nípa ìkọlù agbébọn l‘Ogun sórí ayélujára láti pawó, ọ̀rọ̀ bá bẹ́yìn yọ fún-un
26 Èbibi 2026

Kí ni ká ti pe èyí? Àṣòfin tẹ́lẹ̀, ‘Radical’ fi èpè bọnu níwájú ààfin Olubadan lẹ́yín tó pàdánù tíkẹ́ẹ̀tì
21 Èbibi 2026

Àwọn èèyàn fi àìrọ́mọbí bú mi lójú mi rí-Ooni Ogunwusi
18 Èbibi 2026

Àìsàn ‘sickle cell’ bá mi fínra tó bẹ́ẹ̀, mo bẹ Ọlọrun kó gba ẹ̀mí mi – Adekunle Gold
17 Èbibi 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
- 1Fayose nílò àdúrà, ẹ ṣàánú rẹ̀ – Makinde da padà lẹ́yìn tí Fayose ní ó lè jẹ́ òun ló ṣagbátẹrù ìjínigbé Ogbomoso
- 2Ìjàmbá ọkọ̀ ló fa ikú òṣèré tíátà, ‘Janmole’ – Mr Latin
- 3Aráàlú fárígá, àwọn olùwọ́de já géètì sẹkitéríàtì ìjọba, ìpè fún ìtúsílẹ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l’Ogbomoso káàkiri Nàìjíríà
- 4Èyí làwọn olóṣèlú tó fẹ́ dupò ààrẹ ní 2027 tórúkọ wọn gbilẹ̀ jù
- 5Àwọn ilé ẹ̀kọ́ tilẹ̀kùn wọn pa l’Osun nítorí ìròyìn pé agbébọn wọ ìlú, Adeleke ní kò sí ohun tó jọ bẹ́ẹ̀
- 6Àwọn wo ló fẹ́ wú ère ẹlẹ́sẹ̀ ayò, Lionel Messi, àti pé kí ló fàá?
- 7Aṣọ kan ló kù lọ́rùn àwọn òbí mi nítorí ẹ̀kọ́ mi, ètò ẹ̀yáwókàwé NELFUND ló kó mi yọ láti kẹ́kọ̀ọ́ jáde – Oladepo Gbenga akẹ́kọ̀ọ́ tó mókè jùlọ ní fásitì LAUTECH
- 8”Èyi ni ipa tí Bàba-bàbá mi kó nínú ogun abẹ́lé Biafra”-Meji Alabi, gbajúmọ̀ adarí orin
- 9‘A ò lè lọ síbi iṣẹ́ mọ́ torí àwọn olùkọ́ àtàwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l’Ogbomoso,’ àwọn olùkọ́ ṣèfẹ̀hónúhàn l’Oyo
- 10Àgbà òṣèré tíátà, Feso Oyewole jáde láyé


















